Adunit-12333

Saturday, December 17, 2022

ONAREBU BIODUN AKINLADE DUPE LỌWỌ GÓMÌNÀ DAPỌ ABIODUN, EGBE APC, FUN ADUROTI LORI ÌDÁJỌ ILE ẸJỌ KÒ TÉMI LỌRÙN

 



ÀṢEYỌRÍ GBOGBO WA LÁPAPỌ̀-ÀPILẸ̀KỌ ÌKÍNI LÁTI ỌWỌ́ RT. HON. ABÍỌ́DÚN ISIAQ AKÍNLÀDÉ


Tìdùn

nútayọ̀ àti ìbọláfúnni, mo fi ọpẹ́ ńlá fún Ọlọ́run Ọba, Olóore-Ọ̀fẹ́ Aláàánú-jùlọ, lórí oore ńlá kàǹkà tí Ó ṣe fún mi láti jáwé olúborí ní Ilé-Ẹjọ́-Kò-tẹ́-mi-lọ́rùn, tí ó wà ní ìlú Ìbàdàn, ní èyí tí ìgbẹ́jọ́ ti wáyé lórí ipò tí mo ń díje fún lábẹ́ Ẹgbẹ́ Ìṣèlú All Progressive Congress ní Ẹkùn Gúúsù-Yewa/Ìpókiá fún Ilé-Ìgbìmọ̀ Aṣòfin-Àgbà, nínú ìdìbò Ìjọba Àpapọ̀ tí ń bọ̀ lọ́dún 2023.


Bí ènìyàn bá gùn ẹṣin kọjá nínú mi, kò lè kọsẹ̀, nítorí pé, mo moore púpọ̀ sí Ọlọ́lá-jù-lọ, Ọmọọba Dàpọ̀ Abíọ́dún MFR, tí ó jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ògùn, fún akitiyan àti àtìlẹ́yìn rẹ̀ ní àkókò náà. Gómìnà ni èjìká-tí-kò-jẹ́-kẹ́wù-ó-bọ́ fún mi, ni mo fi gbà pé Adarí rere àti aṣáájú pàtàkì ni o jẹ́.


Mo tún fi ìdùnnú àti ayọ̀ dúpẹ́ lọ́wọ́ Bàbá gbogbo wa, Olóyè Olúṣẹ́gun Ọ̀ṣọbà, mo sì tún kí igbá-kejì Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ògùn, Amojú-Ẹ̀rọ Noimot Sàlàkọ́ àti Ọ̀gbẹ́ni Tàlàbí SSG pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tí wọ́n jẹ́ alánìíyàn rere.


Gbogbo akitiyan àti àtìlẹ́yìn tí àwọn Adarí-Ẹgbẹ́ APC Àpapọ̀ àti Ìpínlẹ̀ Ògùn ṣe fún mi náà kò ṣe é fi ojú parẹ́ nínú àṣeyọrí yìí.


Mo kí àwọn Amòfin tí wọ́n ṣe iṣẹ́ takuntakun láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé ìparí lábẹ́ Amòfin-Àgbà tí ó jẹ́ Kọmíṣánnà fún Ètò-Ìgbẹ́jọ́, ìyẹn Ọ̀gbẹ́ni Olúwaṣínà Ògúngbadé SAN. Oore ńlá gbáà ni o se fún mi. Mo dúpẹ́ dúpẹ́ oo.


Gbogbo ẹ̀yin Ọ̀gá mi, ẹ̀yin àgbààgbà, àti gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ wa ninu Ẹgbẹ́ Àtàtà, APC ti Ẹ̀ka-Ìwọ̀-Oòrùn Ìpínlẹ̀ Ògùn àti Gúúsù-Yewa/Ìpókiá, ni mo rí akitiyan tí gbogbo yín ṣe. Mo dúpẹ́ púpọ̀ lọ́wọ́ yín o.


Gbogbo ẹ̀yin olólùfẹ́ mi, ẹ̀yin alátìlẹ́yìn mi nílé, lóko àti lẹ́yìn odi Nàìjíríà, ẹ̀yin Ìgbìmọ̀ Akínlàdé, ẹ̀yin mọ̀lẹ́bí mi àti gbogbo ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, ẹ̀yin Olùdarí SWAGA, ẹ̀yin olùdarí ìkànnì wa gbogbo, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ yín lọ́kọ̀ọ̀kan. Mo gbọ́dọ̀ dúpẹ́ ní àrà ọ̀tọ̀ lọ́wọ́ gbogbo àwọn Ìyálọ́jà, àwọn oníṣòwò, àwọn oníṣẹ́-ọwọ́, àwọn Amojú-Ẹ̀rọ, gbogbo Ìgbìmọ̀ Lèmọ́mù àti Àlùfáà, Àjọ Ọmọlẹ́yìn-Jésù, àwọn Ìgbìmọ̀ Ọ̀dọ́, àwọn akẹ́kọ̀ọ́, àwọn Olùkọ́, àwọn CDA, àwọn Ọba Aládé, àwọn Baálẹ̀ àti gbogbo àwọn yòókù lápapọ̀. Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo yín fún iṣẹ́ takuntakun tí ẹ ṣe, bí ẹ ti ń pè mí lórí ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀, tí ẹ dá mi lọ́kàn le pé kí n fi ọkàn balẹ̀ àti gbogbo ààwẹ̀ pẹ̀lú àdúrà tí ẹ ṣe fún mi. Oore ńlá gbáà tí ẹ ṣe wọ̀nyí, n ò ní ya aláìmoore oo.


Àṣeyọrí wa ní Ilé-Ẹjọ́-kò-tẹ́-mi-lọ́rùn ni mo fi sọrí Èdùmàrè, gbogbo àwọn tí a jọ díje ní ipele àkọ́kọ́ àti gbogbo àwọn olólùfẹ́ wa nínú ẹgbẹ́ APC.


A ti borí ní ipele àkọ́kọ́ báyìí. Ìṣọ̀kan àti àjùmọ̀ṣepọ̀, àṣeyọrí wa lórí ìdìbò àpapọ̀ ní ọdún 2023 yóò so èso rere. Mo wá rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí gbogbo wa láti gbàgbé gbogbo ohunkóhun yòówù kí ó ti ṣẹlẹ̀ sẹ́yìn, kí a sì ṣe ara wa ní ọ̀kan láti ṣe iṣẹ́ papọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọmọ Ẹgbẹ́ APC kan ṣoṣo. Bí mo bá ti ṣẹ ẹnikẹ́ni nípasẹ̀ ìwà tàbí ohunkóhun, ẹ dákun, ẹ ṣe àmójúfò fún mi, kí ẹ gbà pé Ọlọ́run nìkan ni ó gbọ́n jù lọ.


Gbogbo ẹ̀yin ènìyàn mi ní agbègbè Gúúsù-Yewa/Ìpókiá lábẹ́ Ìjọba Àpapọ̀, mo mọ̀ dájú pé, bí ó ti wù yín láti jẹ́ kí n jáwé olúborí nínú ìdìbò Ìjọba Àpapọ̀ tí ń bọ̀, kí n lè dara pọ̀ mọ́ Ìgbìmọ̀ Aṣòfin-Àgbà, ó fi hàn pé yóò so èso rere fún ìdàgbàsókè lórí ètò ìjọba àwaarawa, tí yóò sì tún pèsè àǹfààní onírúurú àwọn ohun amáyédẹrùn. Bákan náà, bí ẹ ti mọ̀ mí sí Bàbá Ọmọ Kéékèèké, ÌPÈSÈ IṢẸ́ LỌ́PỌ̀LỌPỌ̀ FÚN ÀWỌN Ọ̀DỌ́ WA yóò túbọ̀ wáyé.


Mo gba gbogbo wa ní ìmọ̀ràn láti tú yááyá jáde fún ìpolongo Ẹgbẹ́ wa, APC nínú ìdìbò tí ń bọ̀ lọ́nà yìí. Ẹ jẹ́ kí a fọwọ́ sowó pọ̀ láti borí àwọn Ẹgbẹ́ alátakò wa ní gbogbo ọ̀nà.


Gẹ́gẹ́ bí ẹ ti mọ̀ mí tẹ́lẹ̀, ìwà àti ìṣesí mi náà kò tíì yí padà. Bí mo jẹ́ onítẹríba, aláàánú àti akíkanjú ẹ̀dá fún àṣeyọrí àwọn ènìyàn mi ní Ẹkùn Ìwọ-Oòrùn Ìpínlẹ̀ Ògùn. MO JẸ́JẸ̀Ẹ́ PÉ Ń Ò NÍ DÓJÚ TÌ YÍN NÍ GBOGBO Ọ̀NÀ.


Lẹ́ẹ̀kan sí i, mo dúpẹ́ púpọ̀ lọ́wọ́ gbogbo ẹ̀yin olólùfẹ́ mi. Gbogbo wa pátá ni a jọ ni àṣeyọrí yìí.


Èmi ni tiyín tòótọ́,


Rt. Hon. Abíọ́dún Isiaq Akínlàdé

Olùdìje lábẹ́ Ẹgbẹ́ All Progressive Congress

Fún ipò Aṣojú Ilé-Ìgbìmọ̀ Aṣòfin-Àgbà

Ní Ẹkùn Gúúsù-Yewa/Ìpókiá.


Ẹ ṣeun mi oo.

"WITH UNITY OF PURPOSE AND TOGETHERNESS, OUR VICTORY AT THE GENERAL ELECTION IS CERTAIN": FULL TEXT OF HON. BIODUN AKINLADE THANK YOU MESSAGE AFTER COURT OF APPEAL VICTORY




VICTORY TO ALL - A THANK YOU MESSAGE FROM RT. HON. ABIODUN ISIAQ AKINLADE


With all sense of humility and gratitude, I give glory to Almighty God, the beneficent and the most merciful, for His unfailing mercies on the victory recorded at the Court of Appeal, Ibadan, which upheld my candidacy as the All Progressives Congress flagbearer for Yewa South/Ipokia Federal Constituency, in the 2023 General Elections.


With enormous gratitude in my heart, I extend my profound appreciation to, His Excellency, Prince Dapo Abiodun MFR, the Executive Governor of Ogun State, for his sincere love and support during the period. You gave me a shoulder to lean on, indeed, you are a compassionate leader and brother.


Let me also, in a special way, acknowledge the support of our father, Chief Olusegun Osoba, Deputy Governor, Engr. Noimot Salako Oyedele, Mr. Tokunbo Talabi SSG, and most importantly, the Honourable Commissioner of Justice and Attorney General, Mr. Oluwasina Ogungbade SAN.


The unwavering support and solidarity extended by the APC National and State Executives are well acknowledged and appreciated. 


To our Legal Team, your efforts were outstanding. Thank you exceedingly.


The Leaders, Elders, and members of our GREAT party, APC Ogun West Senatorial District, and Yewa South/Ipokia Federal constituency have been so supportive; I appreciate you all.


To all my supporters, The Abiodun Akinlade Group, my family, friends, SWAGA executives, and the Media, I acknowledge your unique roles. I must also place on record the unwavering support I received from our Market Women, Artisans, Technocrats, League of Imams and Alfas, the Christian Associations, Student Bodies, Community Development Associations, Royal Fathers, Baales, and many more. Thank you all for your calls, prayers, and fasting. Your display of tenacity and capacity is unprecedented.


Our victory at the Court of Appeal is dedicated to Almighty God, all those that contested the primaries with me, and our loyal Party members.


The first hurdle has been crossed. With unity of purpose and togetherness, our victory at the General Election is certain by God's grace. I appeal to all and sundry to let us forget whatever misgivings, and let us work together as a TEAM and member of the same political family. If by an act of omission or commission, I have wronged anyone, kindly forgive, as perfection belongs to Almighty God alone.


My return to the GREEN CHAMBER, as a ranking Member of the Parliament, by God's grace, will guarantee more dividends of democracy, empowerment, developmental projects, and most importantly, as Baba Omokeke, more EMPLOYMENT OPPORTUNITIES FOR OUR TEEMING YOUTHS.


I implore us all to go out and campaign for all the Candidates of our great party, APC, in the forthcoming General Elections. We should join hands to defeat the opposition at the polls.


As always, I remain humble, passionate, and committed to the progress and prosperity of my people in Ogun West. I will continue to MAKE YOU PROUD.


Once again, I deeply express my profound gratitude to everyone. This victory is for ALL.


God bless the good people of Yewa South/Ipokia Federal Constituency 


Yours Sincerely,


Rt. Hon. Abiodun Isiaq Akinlade

Baba Adinni of Yewaland 

All Progressives Congress House of Representatives Candidate,

Yewa South/Ipokia Federal Constituency.

Monday, March 7, 2022

NAIRA RAIN AS AFROGRAMMS OSA CLUB940 DONATES CASH TO TEACHERS AND OUTSTANDING PUPIL OF THEIR ALMA MATA

 




   

As part of the events to mark the 22nd year of graduating from secondary school, the representatives of Klub940, an alumni set of African Church Grammar School, Ita Iyalode, Ogun State, visited the school to make cash presentations to three individuals.

In a release made available to Freelanews and signed by the secretary of Afrograms OSA Club940, Comr. Kamorudeen Adegbokiki, two teachers and a pupil received the cash donations for their relentless efforts in putting the name of the school on world map.

The recipients included the Physics teacher, Peter Ajayi; ICT instructor, Olatunbosun Ganiu and a pupil, Gbolahan Ayinde.

According to the release, Ayinde was singled out for emerging first position at the just concluded JETS competition at Federal Government College, Keffi in Nasarawa State.

“Total cash donation of N600,000.00 (Six Hundred Thousand Naira Only) was presented to Mr. Peter Ajayi (The Physics Teacher), Mr. Olatunbosun Ganiu (The ICT Instructor) and Master. Gbolahan Azeem Ayinde (the pupil that emerged First at the just concluded JETS competition held in Nasarawa earlier this year.) The presentation took place in the Principal Office having the VP admin, the teachers and parents of Master Azeem,” Comrade Adegbokiki wrote.

Speaking on behalf of the president of Club 940, Rotn. Segun Showunmi, informed the school management that the anniversary was like 2years late because the members’ plan was to celebrate 20th of leaving the school.

“The clubset desired to have done something for the school to mark our 20th Anniversary, but for Covid19, we could not match up. We then want to use this moment to commemorate our over 20yrs of leaving the great school that have shaped us to become a better person in our individual chosen careers,” Rotn. Segun Showunmi said.

In his response, the principal of the school appreciated the old students for the gesture, while noting that this will go a long way in encouraging both the pupils and the teachers to strive for more success. He also used the opportunity to appeal to them to always remember the school leadership when showing appreciation such as this.

On their part, the beneficiaries took turn to appreciate the old students for the donations, while assuring the representatives that this will endeared them to their duties and focus more on making the school proud.

The event came to a close after cheques were presented to the recipients

Tuesday, March 1, 2022

"MY DAD WORKED HARD THROUGHOUT HIS PUBLIC SERVICE" ~Dr. Babatunde Diya Extols General Oladipupo Diya Virtues As A Disciplinarian, Lover of Education. Hint on Next Political Steps Ahead Of 2023.

You might not know much about Dr. Tunde Diya, the son of General Oladipo Diya, former Military Administration of Ogun State years back. He is currently in active politics. Though, he contested as a local government chairman, Odogbolu , Ogun State. But he didn’t win. He has started all over again looking at another position to contest for in 2023 general election.

In this interview, Dr. Tunde a medical doctor spoke about his journey in politics, life as a silver spoon son and how General Oladipo Diya waned him not to steal as a politician.

Excerpts :    



Dr. Tunde Diya, it is my pleasure to have you?

You are welcome, Confirm News.

Our readers will want to know what kind of doctor are you?

I am a Medical doctor.

How long have you been practicing?

I have been practicing for about six years now.

I did clinical practice for 3 years but I decided to go into health care service provision and management. That is the space in the Medical field I am currently working in.

Is it private or public?

It is a private company. I set it up with a colleague of mine that we both did our Housemanship in Lagos State University Teaching Hospital (LASUTH) together years back. We thank God, we are progressing.

As someone born with a silver spoon, being that your father was General Oladipo Diya, would you agree that this made you to achieve a lot?

I give Almighty God the glory for the fact that I have a pacesetter as a father and someone that worked hard through out his time in public service especially as Military Administration of Ogun State and even as the youngest platoon commander in Ikeja Military Cantonment. It was also reflective of his cabinet as an Administrator then as most of his appointees were based on merit. He got through his ranks in the prestigious Nigerian Army by merit. He sacrificed thirty-five years in active service for Nigeria. He served Nigeria very well. ‘Heaven helps those who helps themselves’ and God has been faithful, but I think the times have changed. In the South, there is a different mindset entirely. We believe in merit in the South. Someone like me who come from specific backgrounds, people expect us to do more. Even at that, whatever I wanted to do, I always put God first to guide and direct me.

Let us talk about your background, you are originally from Odogbolu, Ogun State but you were born and brought up in Lagos. Is your dad very strict on you while growing up?

No description available.
Dr. Tunde Diya addressing audience at DTDF

Yes, I was born in Lagos. But everyone in Odogbolu knows that every Christmas, we are always at home , inside the family house, Agada area. I always travelled to Odogbolu for extended family events and etc. It has been a culture for me and all of us in the family. Of course since I started my Foundation work and politics, I have been more frequent in Odogbolu.

More so, In the military, they teach you how to be very disciplined. So in every aspect of one’s life, they teach you how to be very focused, determined and disciplined. Yes, my father was very strict. He doesn’t only have ten of us as his children but also had extended family from his older and younger brothers, friends, he chose to be responsible. My Grandfather was the Olugbon of Odogbon in Agada and a railway worker with the Railway Corporation. He wasn’t rich, neither was he poor, but he had many children also. General had to be extremely disciplined and prudent from an early age. He believed without discipline, one will not be able to achieve lots in life. His plan was to educate his entire family and beyond and to God be the glory, he achieved that. Initially, I myself wanted to be a military officer. I admired him a lot. seeing him dressing in military outfit, especially while we were in Abuja, it excited me. But along the line, I had this Aunt, who had a lot of influence on my dad. Her husband was a doctor in the military also; she was equally a nurse. She influenced me towards leaning to medicine. I was in Kings College then. I did JSS 1- 3 there. From there, I moved to Ibadan to finish my secondary school in a private school. My primary to secondary school weren’t all public schools till my move to Ibadan. So suddenly, Medicine just go planted on my mind. Of course, it is a prestigious profession and my dad and mum supported me. I am also working hard to achieve a lot.

Coming into politics, you contested for Odogbolu Local Government Chairmanship position, unfortunately you didn’t win, did you have your dad’s support. Lots of people reacted that you should have won being the son of former military governor of Ogun State?

No description available.
Dr. Tunde Diya attending to old women health care in Odogbolu

Before I started politics, I went to him for his blessings. He asked me why I was going into politics, if it was for going sake or if I had a passion for doing things differently in politics? He also asked that are you sure you are not going into politics to embezzle money? I wasn’t shocked as I had heard him on numerous occasions speak about the need for people to want to serve without ‘ojukokoro’ like they say. He is completely against corruption and laziness in public office holders. A lot of people who know him will tell you he has always been very blunt about this. To God be the glory, while he was the Military Administrator of Ogun State, or Vice President and after, there has not been any case or issue as to this regard. He was and is still a very contented man.

What was your reaction when you contested for Odogbolu Local Government Chairman but it didn’t go your way?

The truth is when I ventured into Politics, I looked around me, there was something about APC that inspired me. APC is a party that provided the platform for Nigerian youth to showcase themselves. APC gives the youth that opportunity to effect the desired change into Nigerian politics. The Electoral Act ( Amendment ) bill just passed by President Muhammadu Buhari GCFR is exciting the youth right now, more confidence has been built amongst the electorates, voter registration may increase, the technology world is booming with Hundreds of Millions of US Dollars pouring into our economy which is a very youth friendly sector, attractive to the generation Z we may need to handle with a lot of care , unlike the health care sector where that’s a sector more appealing to the older generation. All this happening in an APC-led government. So I came in with that passion to make a difference. I set up the Doctor Tunde Diya Foundation (DTDF) with The Yellow initiative (TYI ). The Yellow Initiative particularly was set up to support His Excellency, Prince Dapo Abiodun, MFR and the people of Ogun State which is a continuous process. If people collectively support a government, things will move forward for all of us. So for my people and I, the main focus of seeking public office is to deliver the dividends of democracy to the people which is engraved in my heart permanently with a mindset of the need to implement policies that will benefit people. I decided to focus on starting at the Local Government level. A leader in the APC once told me “Politics is from bottom to the top”, I took it as a good advice and it stuck, that’s why I started from the Local Government Level. A lot of my friends, colleagues, supporters were shocked and felt Local Government was low for me. I thanked them for holding me in high regard but I disagreed with them. To me it has never been about high or low. It has always been about treating the fundamental issues which stem majorly from the grassroots. Tackling it at that point will alleviate a lot from the socio-economic issues and etc. So not winning that election will never stop me from pursuing my goals and agenda to improve the lives of the people of Odogbolu or Ogun State as a whole. The foundation is still on going, the Yellow Initiative is still 100% active with the Environmental Upkeep and Upgrade Work, Health Care Project and the Free Education Work with a lot still planned even after the Elections. It is simply not my work or within my power but Gods work and I am just his servant and messenger.

No description available.
Dr. Tunde Diya posses